BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ọkùnrin kan jábọ́ láti orí ilé alájà mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, Cocoa House nílùú Ibadan
Iṣẹlẹ yii mu idaduro ba ọpọ okoowo to wa ni agbegbe naa lọjọ Aje
Fídíò, Wo bí o ṣe le dífá lọ́dọ́ babalawo láti orí fóònù rẹ láti ibikíbi l'ágbàáyé, Duration 1,23
Olawole Olakunle, Babalawo to n jatọ ba BBC sọrọ lori ipa ti imọ ẹrọ n ko ibamu pẹlu Ifa ati awọn nnkan aṣa miiran.
Fídíò, 'Gbogbo ìpèníjà ètò ààbò yóò di ìgbàgbé nílùú Owo tá a bá rí irinṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ', Duration 7,35
Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Wilfred Olutokunbo Afolabi sọrọ lori awọn aṣeyọri ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, ati awọn ipenija wọn
'Omijé ni mo fi n wẹ ibùsùn mi lálaalẹ́ láti ìgbà tí ìgbéyàwó mi ti túká'
Biola Adebayo sọ pe igbeyawo oun ti tuka
Ta ló lẹ́tọ̀ọ́ láti pa ẹran Ileya?
Ileya jẹ́ ọdún tó ṣe pàtàkì sáwọn Mùsùlùmí nítorí òhun ni wọ́n kà kún ọdún ńlá níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran àgbò.
Èèyàn tó ti pàdánù ẹ̀mí wọn níbi ẹ̀kún omi Niger ti di 230, 400 di àwátì
Iṣẹlẹ omiyale yii ni igbagbọ wa pe oun lo buru ju lorilẹede Naijiria, laarin aadọta ọdun.
Fídíò, 'Àwọn èèyàn ma n sá, wọ́n sì má n bẹ̀rù ẹbí mi nítorí Trichoepithelioma tó mú wa', Duration 4,30
Mọlẹbi to ni aisan Trichoepithelioma, aisan kan to ma n ran ninu ẹbi, ba BBC Yoruba sọrọ lori iriri wọn
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,01
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbàyé tí kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Ó kéré tán, aláboyún kan ló n kú láàrin ìṣẹ́jú méjé síra wọ́n lásìkò ìbímọ̀ ní Naijiria
Nàìjíríà ni orílẹ̀ èdè tó léwu jùlọ ní àgbáyé láti bímọ sí pẹ̀lú àkọ́ọ́lẹ̀ ìdá mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29%) àwọn obìnrin tó pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò ìbímọ káàkiri àgbáyé.
Wo ìlú tó ti jẹ dandan fún ọkọ láti rà kẹ̀kẹ́ fún ìyàwó kí ìgbeyàwó tó ó le wáyé
Nibi ti kẹkẹ gbayi de lọdọ awọn obinrin Askira, dandan ni ki ọkunrin to ba fẹẹ fẹ wọn ra kẹkẹ mọ ẹru obinrin ti yoo gbe niyawo.
Ìdí tí àkọọ́lẹ̀ 'writing' àwọn dókítà ò fi kí n dùn ún wò tí kìí sí yé èèyàn
Kíkọ nǹkan sílẹ̀ ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ojú àti ẹ̀yà ara tó wà fún ara yíyí.
Ojú mi ni omi ṣe wọ́ ìyàwó àti ọmọ mi lọ, èèyàn mẹ́sàn-án ni èmi nìkan pàdánù nínú ẹ̀kún omi Mokwa'
Ọmọ kan ṣoṣo naa ni Adamu ṣẹṣẹ bi, o ṣalaye fun BBC pe ọmọ ikoko naa pẹlu iya rẹ to bi i foun, wa lara awọn eeyan ti omi wọ lọ latari ojo nla to rọ l'Ọjọruu mọju Ọjọbọ, nipinlẹ Niger. Eyi to fa omiyale ati ẹkun omi to bo ori awọn ile lọ.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Òbí sọ ọ̀gá ilé-ẹ̀kọ́ di èèrò iléèwòsàn lẹ́yìn tí kò jẹ́ kí ọmọ rẹ̀ jìwèé wò nínú ìdánwò WAEC l'Akure
Iwadii BBC YORUBA ṣafihan pe akẹkọọ naa, Elisha Wisdom n gbiyanju lati lo ẹrọ ilewọ rẹ lasiko ti ọgbẹni Rotifa gba ẹrọ ilewọ naa eyi to mu ki inu bi iya ọmọ ọhun gidigidi.
Iléeṣẹ́ ológun ṣèèṣì ju àdó olóró sáwọn aráàlú, àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ní kí ìjọba ṣe ìwádìí
Àwọn aráàlú ní ìpínlẹ̀ náà sọ pé ogún èèyàn ló pàdánù ẹ̀mí wọn nígbà tí iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà fi ọkọ̀ òfurufú ju àdó olóró sí ìlú náà láti fi lásìkò tí wọ́n ń gbìyànjú láti kojú ìjà sáwọn agbébọn tó wà ṣe ìkọlù sí wọn.
Afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pàdé ikú òjijì lẹ́yìn eégún l'Osogbo
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, DSP Abiodun Ojelabi, ṣalaye fun BBC Yoruba wi pe awọn ẹlẹgbe okunkun lo ọdun egungun to waye lagbegbe Oke Ola niluu Osogbo lati ṣe ikọlu si ara wọn.
'Inú yàrá ni mo tẹ́ ọmọ oṣù méjì mi sí àmọ́ inú kàǹga la ti rí òkú rẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta'
Nigba to n ba BBC News Yorùbá sọrọ Aishat Tahiru sọ pe, lọjọ Kẹẹdọgbọn, osu Karun un ni oun tẹ ọmọ oun to jẹ ọmọ oṣu meji ti orukọ rẹ n jẹ Adam Tahiru sinu yara lati sun, ti oun si lọ kirun lẹyinkule.
Ọkunrin ọmọ India tó kó ejò olóró mẹ́tàdínláàdọ́ta wọ ìlú kó sí gbaga àjọ aṣọ́bodè
Ọkunrin ọmọ India tó kó ejò olóró mẹ́tàdínláàdọ́ta wọ ìlú kó sí gbaga àjọ aṣọ́bodè
'Pẹ̀lú ìbùsùn ní omí gbé ọ̀pọ̀ èèyàn lọ, kódà ọmọ ìyá kan nàá mẹ́rin wà lára wọn'
Ko din ni aadọfa eeyan ti omi gbe lọ, ti ọpọ eeyan si di alainilelori lẹyin ti agbara ojo ya wọ ile wọn nipinlẹ Niger
Bàbá yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn tó rò pé ọ̀bọ ni òun rí nínú oko l'Ekiti
Iroyin ni ṣẹ ni ọkunrin naa ṣeṣi yinbọn pa ọmọ rẹ ọhun to jẹ ọmọ ọdun marundinlogun latari bi awọn ọbọ ṣe maa n da a lamu ninu oko rẹ.
Awuyewuye lórí àwọn èèyàn tí Tinubu ń yàn sípò
Awuyewuye ń pọ̀ si látàrí báwọn èèyàn tí Tinubu ń yàn sípò tó ṣe kókó ṣe ń jẹ́ ẹ̀yà Yorùbá.
Ìtàn ayé Baṣọ̀run Gáà, ìjòyè tó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á
Ìtàn ìgbé ayé Baṣọ̀run Gáà, gbájúmọ́ ìjòyè tó pa Aláàfin mẹ́rin
Nǹkan márùn-ún tó ṣe é ṣe kí o má mọ̀ nípa Hajj
Hajj jẹ ọkan ninu akojọpọ awọn ẹlẹṣin to pọ julọ lagbaye, ti ọpọ eeyan si n wa si bẹ lati origun mẹrin agbaye lati ṣe iṣẹ Hajj.
Nǹkan mẹ́jọ tó le mú kí obìnrin má rì í nǹkan oṣù láì lóyún
Tí obìnrin kò bá rí nǹkan oṣù rẹ̀ láàárín ọjọ́ péréte tàbí tí ọjọ́ tó yẹ kó ri bá lé díẹ̀, ó ṣeéṣe kó má jẹ̀ ẹ́ ohun tó nira àmọ́ tó bá ń léra ní gbogbo ìgbà, ó nílò àmójútó, ó sì lè jẹ́ àmì àpẹẹrẹ àìsàn kan tàbí òmíràn.
Ìjàmbá ọkọ̀ pa eléré ìdárayá bí ogún lẹ́yìn tí wọ́n kúrò ní Gateway Games 2025
Eeyan mọkanlelogun lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye lẹyin ti wọn kuro nipinlẹ Ogun.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Móríwú
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Obìnrin tó lu ọmọ ara rẹ̀ ní gbànjo rí ẹ̀wọ̀n gbére he
Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe oun ko ni dẹkun ati maa wa ọmọde naa bo tilẹ jẹ pe awọn to ta ti gba idajọ to yẹ wọn.
Kí nídìí táwọn obìnrin kan fi máa ń jẹ olubi ọmọ lẹ́yìn ìbímọ?
Àwọn kan gbàgbọ́ pé àwọn èròjà aṣaralóore wà nínú olubi ọmọ èyí tí ọmọ ń gbà lára ìyá rẹ̀ nínú oyún àti pé kò yẹ káwọn èròjà náà ṣòfò lẹ́yìn tí ọmọ bá dáyé tán.
Ilé ẹjọ́ kan gógó bí ìyá tó ta ọmọ rẹ̀ ṣe gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére
Ojiji ni Joshlin Smith, ọmọ ọdun mẹfa ti wọn ni iya rẹ lo ta a di awati nita ile wọn to wa ni Saldanha Bay, nitosi Cape Town.
Wo kókó ohun márùn-ún tí Seyi Makinde ṣe tí ayé ṣe ń fẹ́ ẹ áti èyí tó mú kí wọn korò ojú sí i láàrin ọdún mẹ́fà tó ti wà nípò gómìnà l'Oyo
BBC Yoruba se akojọpọ koko ohun marun ti awọn araalu n yonbo gomina Seyi Makinde fun laarin ọdun mẹfa to ti gori aleefa gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Oyo ati eyi to mu ki wọn koro oju si i.
Níbo láwọn dúkìá tí àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ ń gbà lọ́wọ́ àwọn olóṣèlú wà?
Laipẹ yii ni ijọba gbe ẹsẹ le dukia ile gbe to pọ ti Gomina tẹlẹ fun banki apapọ, Godwin Emefiele kọ kalẹ.
Iye èèyàn tí àgbàrá omi gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Niger tí lé ní 150
Iroyin yii lo n waye lẹyin ti Aarẹ Bola Tinubu paṣẹ pe ki NEMA ṣe ibudo kan sagbegbe naa lati maa doola awọn ti iṣẹlẹ naa pa lara julọ.
Ọwọ́ ológun Nàìjíríà tẹ ṣọ́ja 18, ọ̀lọ́pàá 15, fẹ̀sùn kan àwọn àjọ òkèèrè tó ń ṣe agbódegbà fáwọn agbésùnmọ̀mí
Ileeṣẹ ologun ni owo ti iye rẹ n wọ ẹgbẹlẹgbẹ dọla ni wọn ba ninu aṣuwọn ifowopamọ awọn afurasi naa
Regina Chukwu sọ ìdí tí ọkọ rẹ̀ ṣe ní kò gún òun ní abẹ́rẹ́ ikú lẹ́yìn ọdún mẹ́tà ìgbéyàwó àti oṣù mẹ́rin tó bímọ
Regina Chukwu sọ pe ni kete ti oun pari ile ẹkọ girama ni oun pade ọkọ oun to jẹ ẹya Igbo nipinlẹ Anambra.
WAEC tọrọ àforíjìn lórí báwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣe kọ ìdánwò nínú òkùnkùn, ilé aṣojú-ṣòfin ké sí WAEC láti sọ tẹnu rẹ̀
Atẹjade ti agbẹnusọ ajọ WAEC, Moyosola Adesina fi lede ni ajọ naa gba pe asise wa lati ọwọ oun eyi to mu ki awọn akẹkọọ joko se idanwo ninu okunkun.
Kàyééfì! Aláboyún tó ní ilé ọmọ méjì, bí ọmọ méjì láàrin ọjọ́ méjì
Onimọ sayẹnsi salaye pe atọ meji ọtọọtọ lo ro papọ mọ ẹyin meji ọtọọtọ to pada doyun ninu iya wọn.